Yemi Osinbajo nikan lo ye lati dari orilede Naijiria ni odun 2023 Ogagun Babangida lo so be


 Ogagun feyinti Ibrahim Badamasi Babangida ninu atejade kan to se loni lo ti fi han wipe igbakeji Aare Orilede Yemi Osinbajo nikan ni eni ti o ye lati dari orilede Naijiria gege bi Aare orilede ni odun 2023. 

O so eleyi nigba ti awon ton se agbateru eto iponlongo eto idibo fun Osinbajo lo se abewo si ni ile re to wa ni ilu Minna.


Atejade na ni yi ni ede geesi;


“Osinbajo has great passion for Nigeria, he is one that can communicate with the country and inspire people among other qualities; he is the best person to lead Nigeria in 2023.

I know the vice president very well; he is a good man; a man who has conviction about Nigeria; a man who can communicate with the country and inspire people.

Such a man is worthy person to work with; we need good man to lead Nigeria; a man who has passion for this country’s economy; Nigeria is a good country; the people of Nigeria are good.

You must learn to understand people and constant discussion is key; I want to convey my best wishes to the vice president through you and I want you to tell him to stay the course; I know it’s not easy but he has the conviction; I wish him the best” he said

 



Comments